Nike Okundaye, Jimi Solanke & More Elevate Yoruba Culture at Ethnic Fashion Show and Awards Night

0

Ibi orí da ni sí l’àágbé mò n s’opé

Orí dá wa ní Yorùbá e yò sèsè

Jéjé ni mo n bò wá s’ílé ayé

kí èyà Yorùbá tó pè mí yá

wàrà nwéré mo ba ara mi nínú àsà àt’ìse to péye

A dé ayé a ba ara wa nílè omo Òoduà atèwòròn

Bi a se n sògo bé ‘e náà là n dúpé lowó orí wa àpéré

Iyìn ni fún èdá mi tí kò so ‘mí lókò s’áàrín èyà míràn

Ìdùnnú ló jé fún mi wípé Yorùbá kò kèrè lónàkonà

Yorùbá ni mí mo lè yagàn Ogbón nbè èníyàn wà. – Dèhìndé Ìdòwú

Where one is destined to be is where one stays

We are destined to be Yorùbá, please rejoice

I was simply coming to the world

And the Yorùbás beckoned me to come over

Swiftly I found myself in a rich culture and tradition

We came to the world and found ourselves in the land of Odùduwà

We were glorifying and blessing our beings, our destinies

We bless the creator for not sending us to another land

It is joyful to me that Yorùbá cannot be underestimated

I am Yorùbá and I can be proud of it Wisdom and people abound.

The Yoruba Arts and Festivals Promotion Limited created a magical night at the Ripples Hotel, Osogbo on Thursday 20th August 2015. The maiden edition of the Ethnic Fashion Show and Awards Night was held on the eve of the finale of the Osun – Osogbo Festival. The cultural fiesta started off with notable dignitaries present including Oba Dokun Abolarin, Oba Adeen Adedapo Aderemi, Babajide Omoworare, Tunde Fagbenle, Jimi Solanke, Gboyega Adelaja, Yomi Layinka, Tunde Adegbola, Doyin Adunni Olorisa, Tunde Oshinibosi, Teju Kareem, Hugh and Robin Campbell.

Please view the gallery below:

Get more stuff like this
in your inbox

Subscribe to our mailing list and get interesting stuff and updates to your email inbox.

Thank you for subscribing.

Something went wrong.

Leave a Reply Cancel reply